a
Ro 2.24
.
Isaiah 52:5
5
a
“Àti ní àkókò yìí, kí ni mo ní níbí?” ni
Olúwa
wí.
“Nítorí a ti kó àwọn ènìyàn mi lọ lọ́fẹ̀ẹ́,
àwọn tí ó sì ń jẹ ọba lórí wọn fi wọ́n ṣẹlẹ́yà,”
ni
Olúwa
wí.
“Àti ní ọjọọjọ́
orúkọ mi ni asọ̀rọ̀-òdì sí nígbà gbogbo.
Copyright information for
YorBMYO